Jẹnẹsisi 11:20-24 BIBELI MIMỌ (BM)

20. Nígbà tí Reu di ẹni ọdún mejilelọgbọn ni ó bí Serugi.

21. Ó tún gbé igba ọdún ó lé meje (207) sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Serugi, ó sì tún bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.

22. Nígbà tí Serugi di ẹni ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Nahori.

23. Ó tún gbé igba (200) ọdún sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Nahori, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.

24. Nígbà tí Nahori di ẹni ọdún mọkandinlọgbọn ni ó bí Tẹra.

Jẹnẹsisi 11