Àwọn Ọba Kinni 11:41-43 BIBELI MIMỌ (BM)

41. Àwọn nǹkan yòókù tí Solomoni ṣe: gbogbo iṣẹ́ rẹ̀, ati ọgbọ́n rẹ̀, ni a kọ sinu Ìwé Ìṣe Solomoni.

42. Ogoji ọdún ni ó fi jọba lórí gbogbo Israẹli ní Jerusalẹmu.

43. Nígbà tí ó kú, wọ́n sin ín sí ìlú Dafidi, baba rẹ̀, Rehoboamu, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.

Àwọn Ọba Kinni 11