Àìsáyà 40:1-3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ẹ tùú nínú, ẹ tu ènìyàn mi nínú,ni Ọlọ́run yín wí.

2. Sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ fún Jérúsálẹ́mùkí o sì kéde fún unpé iṣẹ́ àṣekára rẹ̀ ti parí,pé à ti san gbésè ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,pé ó ti rí i gbà láti ọwọ́ Olúwaìlọ́po méjì fún gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

3. Ohùn ẹnìkan tí ń pè:“Nínú ihà ẹ pèṣèọ̀nà sílẹ̀ fún Olúwa:ṣe é kí ó tọ́ ní ihàòpópónà fún Ọlọ́run wa.

Àìsáyà 40