Sakaraya 7:1 BIBELI MIMỌ (BM)

Ní ọjọ́ kẹrin oṣù kẹsan-an, tíí ṣe oṣù Kisilefi, ní ọdún kẹrin ìjọba Dariusi, ni OLUWA rán mi níṣẹ́ yìí.

Sakaraya 7

Sakaraya 7:1-10