Jẹnẹsisi 14:8 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà náà ni ọba Sodomu, ati ọba Gomora jáde lọ, pẹlu ọba Adima, ọba Seboimu, ati ọba Bela, (tí ó tún ń jẹ́, Soari). Wọ́n pa ogun wọn pọ̀ ní àfonífojì Sidimu.

Jẹnẹsisi 14

Jẹnẹsisi 14:7-17