Ìṣe Àwọn Aposteli 17:29 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí a jẹ́ ọmọ Ọlọrun, kò yẹ kí á rò pé Ọlọrun dàbí ère wúrà, tabi fadaka, tabi òkúta, ère tí oníṣẹ́ ọnà ṣe pẹlu ọgbọ́n ati èrò eniyan.

Ìṣe Àwọn Aposteli 17

Ìṣe Àwọn Aposteli 17:23-34