Àwọn Adájọ́ 8:24 BIBELI MIMỌ (BM)

Ṣugbọn ó rọ̀ wọ́n pé kí olukuluku wọn fún òun ní yẹtí tí ó wà ninu ìkógun rẹ̀, nítorí pé àwọn ará Midiani a máa lo yẹtí wúrà gẹ́gẹ́ bí àwọn ará ilẹ̀ Iṣimaeli yòókù.

Àwọn Adájọ́ 8

Àwọn Adájọ́ 8:19-26