2. A. Ọba 9:28 Yorùbá Bibeli (YCE)

Awọn iranṣẹ rẹ̀ si gbé e ninu kẹkẹ́ lọ si Jerusalemu, nwọn si sìn i ni bojì rẹ̀ pẹlu awọn baba rẹ̀ ni ilu Dafidi.

2. A. Ọba 9

2. A. Ọba 9:22-35