Samuẹli Kinni 9:25 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá sinu ìlú láti ibi ìrúbọ náà, wọ́n tẹ́ ibùsùn kan fún Saulu lórí òrùlé, ó sì sùn sibẹ.

Samuẹli Kinni 9

Samuẹli Kinni 9:19-27