Samuẹli Keji 15:10 BIBELI MIMỌ (BM)

Ṣugbọn Absalomu rán iṣẹ́ àṣírí sí gbogbo ẹ̀yà Israẹli, ó ní, “Tí ẹ bá gbọ́ tí wọ́n fọn fèrè, kí ẹ sọ pé, ‘Absalomu ti di ọba ní Heburoni.’ ”

Samuẹli Keji 15

Samuẹli Keji 15:3-14