Samuẹli Keji 11:7 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí Uraya dé, Dafidi bèèrè alaafia Joabu ati ti gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀. Ó bèèrè bí ogun ti ń lọ sí.

Samuẹli Keji 11

Samuẹli Keji 11:6-17