Orin Dafidi 120:1-2 BIBELI MIMỌ (BM)

1. OLUWA ni mo ké pè, nígbà tí mo wà ninu ìpọ́njú,ó sì dá mi lóhùn.

2. OLUWA, gbà mí lọ́wọ́ àwọn èké,ati lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́tàn.

Orin Dafidi 120