Nọmba 13:7-16 BIBELI MIMỌ (BM)

7. láti inú ẹ̀yà Isakari, ó rán Igali, ọmọ Josẹfu;

8. láti inú ẹ̀yà Efuraimu, ó rán Hoṣea ọmọ Nuni;

9. láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ó rán Paliti, ọmọ Rafu;

10. láti inú ẹ̀yà Sebuluni, ó rán Gadieli, ọmọ Sodi;

11. láti inú ẹ̀yà Josẹfu, tí í ṣe ẹ̀yà Manase, ó rán Gadi, ọmọ Susi;

12. láti inú ẹ̀yà Dani, ó rán Amieli, ọmọ Gemali;

13. láti inú ẹ̀yà Aṣeri, ó rán Seturu, ọmọ Mikaeli;

14. láti inú ẹ̀yà Nafutali, ó rán Nahibi ọmọ Fofisi;

15. láti inú ẹ̀yà Gadi, ó rán Geueli ọmọ Maki.

16. Orúkọ àwọn ọkunrin tí Mose rán láti lọ ṣe amí ilẹ̀ náà nìyí. Mose sì yí orúkọ Hoṣea ọmọ Nuni pada sí Joṣua.

Nọmba 13