Kronika Kinni 19:15 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé àwọn ará Siria sá, àwọn náà sá fun Abiṣai, wọn sì wọ ìlú wọn lọ. Joabu bá pada sí Jerusalẹmu.

Kronika Kinni 19

Kronika Kinni 19:14-19