Johanu 6:14 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí àwọn eniyan rí iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe, wọ́n ní, “Dájúdájú, eléyìí ni wolii Ọlọrun náà tí ó ń bọ̀ wá sí ayé.”

Johanu 6

Johanu 6:4-24