Jobu 31:24-27 BIBELI MIMỌ (BM)

24. “Bí mo bá gbójú lé wúrà,tí mo sì fi ojúlówó wúrà ṣe igbẹkẹle mi,

25. bí mo bá ń yọ̀ nítorí pé mo ní ọrọ̀ pupọ,tabi nítorí pé ọwọ́ mi ti ba ọpọlọpọ ohun ìní.

26. Tí mo bá ti wo oòrùn nígbà tí ó ń ràn,tabi tí mo wo òṣùpá ninu ẹwà rẹ̀:

27. tí ọkàn mi fà sí wọn;tí mo sì tẹ́wọ́ adura sí wọn.

Jobu 31