Jẹnẹsisi 45:8 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí náà, kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbé mi dé ìhín, Ọlọrun ni, ó sì ti fi mí ṣe baba fún Farao, ati oluwa ninu gbogbo ilé rẹ̀ ati alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ijipti.

Jẹnẹsisi 45

Jẹnẹsisi 45:6-14