Jẹnẹsisi 4:1 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí ó yá, Adamu bá Efa, aya rẹ̀, lòpọ̀, ó lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan. Ó ní, “Pẹlu ìrànlọ́wọ́ OLUWA, mo ní ọmọkunrin kan,” ó sọ ọmọ náà ní Kaini.

Jẹnẹsisi 4

Jẹnẹsisi 4:1-5