Jẹnẹsisi 19:29 BIBELI MIMỌ (BM)

Ọlọrun ranti Abrahamu, nígbà tí ó pa àwọn ìlú tí ó wà ní àfonífojì náà, níbi tí Lọti ń gbé run, ó yọ Lọti jáde kúrò ninu ìparun.

Jẹnẹsisi 19

Jẹnẹsisi 19:20-33