Ìṣe Àwọn Aposteli 23:9 BIBELI MIMỌ (BM)

Ni ariwo ńlá bá bẹ́ sílẹ̀. Àwọn amòfin kan ninu àwọn Farisi dìde, wọ́n tẹnu mọ́ ọn pé, “Àwa kò rí nǹkan burúkú tí ọkunrin yìí ṣe. Bí ó bá jẹ́ pé ẹ̀mí ni ó sọ̀rọ̀ fún un ńkọ́? Tabi angẹli?”

Ìṣe Àwọn Aposteli 23

Ìṣe Àwọn Aposteli 23:5-10