Ìṣe Àwọn Aposteli 1:4 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí ó wà lọ́dọ̀ wọn, ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn má kúrò ní Jerusalẹmu. Ó ní, “Ẹ dúró títí ìlérí tí Baba mí ṣe yóo fi ṣẹ, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gbọ́ tí mo sọ fun yín.

Ìṣe Àwọn Aposteli 1

Ìṣe Àwọn Aposteli 1:1-11