Hagai 2:5 BIBELI MIMỌ (BM)

Gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí mo ṣe fun yín, nígbà tí ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, mo wà láàrin yín; nítorí náà, ẹ má ṣe bẹ̀rù.’

Hagai 2

Hagai 2:1-7