Àwọn Ọba Kinni 22:52 BIBELI MIMỌ (BM)

Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ burúkú Ahabu, baba rẹ̀, ati ti Jesebẹli, ìyá rẹ̀, ati ti Jeroboamu, ọmọ Nebati, àwọn tí wọ́n jẹ́ kí Israẹli dẹ́ṣẹ̀.

Àwọn Ọba Kinni 22

Àwọn Ọba Kinni 22:46-53