Àwọn Ọba Kinni 17:14 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí ohun tí OLUWA Ọlọrun Israẹli wí ni pé, ìyẹ̀fun kò ní tán ninu ìkòkò rẹ, bẹ́ẹ̀ ni kólòbó òróró rẹ kò ní gbẹ títí tí OLUWA yóo fi rọ òjò sórí ilẹ̀.”

Àwọn Ọba Kinni 17

Àwọn Ọba Kinni 17:8-20