Àwọn Ọba Kinni 15:3 BIBELI MIMỌ (BM)

Gbogbo irú ẹ̀ṣẹ̀ tí baba Abijamu dá, ni òun náà dá. Kò fi tọkàntọkàn ṣe olóòótọ́ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀ bí Dafidi, baba ńlá rẹ̀ ti ṣe.

Àwọn Ọba Kinni 15

Àwọn Ọba Kinni 15:1-4