Àwọn Ọba Kinni 1:6 BIBELI MIMỌ (BM)

Adonija yìí ni wọ́n bí tẹ̀lé Absalomu, ó jẹ́ arẹwà ọkunrin; baba rẹ̀ kò sì fi ìgbà kan dojú kọ ọ́ kí ó bá a wí nítorí ohunkohun rí.

Àwọn Ọba Kinni 1

Àwọn Ọba Kinni 1:1-13