Àwọn Ọba Keji 19:19 BIBELI MIMỌ (BM)

Nisinsinyii OLUWA Ọlọrun wa, jọ̀wọ́ gbà wá lọ́wọ́ Asiria kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ayé lè mọ̀ pé ìwọ OLUWA nìkan ni ỌLỌRUN.”

Àwọn Ọba Keji 19

Àwọn Ọba Keji 19:10-23