Àwọn Adájọ́ 8:11 BIBELI MIMỌ (BM)

Ọ̀nà èrò tí ó wà ní ìlà oòrùn Noba ati Jogibeha ni Gideoni gbà lọ, ó lọ jálu àwọn ọmọ ogun náà láì rò tẹ́lẹ̀.

Àwọn Adájọ́ 8

Àwọn Adájọ́ 8:3-17