Àwọn Adájọ́ 3:27 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí fọn fèrè ní agbègbè olókè Efuraimu. Àwọn ọmọ Israẹli bá tẹ̀lé e lẹ́yìn láti agbègbè olókè, ó sì ṣiwaju wọn.

Àwọn Adájọ́ 3

Àwọn Adájọ́ 3:19-28