Àwọn Adájọ́ 19:21 BIBELI MIMỌ (BM)

Baba náà bá mú wọn lọ sí ilé rẹ̀, ó fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn ní koríko. Wọ́n ṣan ẹsẹ̀ wọn, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu.

Àwọn Adájọ́ 19

Àwọn Adájọ́ 19:12-27