Sáàmù 58:8-11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

8. Jẹ́ kí wọn rí bí ìgbín tí Rẹ̀ dànù tí ó sì ṣègbébí ọmọ ti oṣu Rẹ̀ kò pé, kí wọn má ṣe rí òòrùn.

9. Kí ìkòkò yín kì o tó mọ̀ ìgbóná ẹ̀gún;ìbá tutù, ìbá ma jò, yóò fi ìjì gbá wọn lọ.

10. Olódodo yóò yọ nígbà a bá ń gbẹ̀san wọnnígbà tí wọn bá wẹ ẹsẹ̀ wọn nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn búburú.

11. Àwọn ènìyàn yóò wí pé,“lóòtọ́ èrè àwọn ń bẹ fún olódodo;lóòtọ́ òun ni Ọlọ́run tí ń ṣe ìdájọ́ ní ayé.”

Sáàmù 58