Sáàmù 144:8-11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

8. Ẹnu ẹni tí ó kún fún èkéẹni tí ọwọ́ ọ̀tún Rẹ̀ jẹ́ ìrẹ́jẹ.

9. Èmi yóò kọ orin túntún sí ọỌlọ́run; lára ohun èlò orinolókùn mẹ́wàá èmi yóòkọ orin sí ọ

10. Sí ẹni tí ó fún àwọn ọba ní ìsẹ́gun,ẹni tí ó gba Dáfídì ìránṣẹ́ Rẹ̀lọ́wọ́ pípanirun.

11. Gbàmí kí ó sì yọ mí nínú ewukúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjìtí ẹnu wọn kún fún èké,tí ọwọ́ ọ̀tún wọn jẹ́ ọwọ́ ọ̀tún èké.

Sáàmù 144