Onídájọ́ 8:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Gídíónì gba ọ̀nà tí àwọn dáràndáràn máa ń rìn ní apá ìhà ìlà oòrùn Nóbà àti Jógíbíà ó sì kọjú ogun sí àwọn ọmọ ogun náà nítorí wọ́n ti túra sílẹ̀.

Onídájọ́ 8

Onídájọ́ 8:5-18