Onídájọ́ 6:9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Mo gbà yín kúrò nínú agbára Éjíbítì àti kúrò ní ọwọ́ gbogbo àwọn aninilára yín. Mo lé wọn kúrò ní iwájú yín, mo sì fi ilẹ̀ wọn fún yín.

Onídájọ́ 6

Onídájọ́ 6:5-16