Onídájọ́ 11:27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Èmi kọ́ ni ó ṣẹ̀ ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ ni ó ṣẹ̀ mí nípa kíkógun tọ̀ mí wá. Jẹ́ kí Olúwa olùdájọ́, ṣe ìdájọ́ lónìí láàárin àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti àwọn ará Ámónì.”

Onídájọ́ 11

Onídájọ́ 11:19-35