18. Ilé Jákọ́bù yóò sì jẹ́ ináàti ilé Jósẹ́fù ọwọ́ ináilé Ísọ̀ yóò jẹ àkékù koríkowọn yóò fi iná sí i,wọn yóò jo run.Kì yóò sí ẹni tí yóò kù ní ilé Ísọ̀.”Nítorí Olúwa ti wí i.
19. Àwọn ará Gúsù yóò ni òkè Ísọ̀,àwọn ará ẹsẹ̀ òkè yóò niilẹ̀ àwọn ará Fílísítíánì ní ìní.Wọn yóò sì ni oko Éfúráímù àti Samáríà;Bẹ́ńjámínì yóò ní Gílíádì ní ìní.
20. Àwọn ìgbèkùn Ísírẹ́lì tí ó wà níKénánì yóò ni ilẹ̀ títí dé Séréfátì;àwọn ìgbékùn láti Jérúsálẹ́mùtí ó wà ní Séfárádìyóò ni àwọn ìlú Gúsù ní ìní
21. Àwọn olùgbàlà yóò sì gòkè Síónì wáláti jọba lé orí àwọn òkè Ísọ̀.Ìjọba náà yóò sì jẹ́ ti Olúwa.