Nọ́ḿbà 9:21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìgbà mìíràn ìkúùkù lè dúró láti ìrọ̀lẹ́ di àárọ̀, nígbà tó bá sì kúrò ní àárọ̀, wọn ó gbéra. Ìbá à ṣe ní ọ̀sán tàbí òru, ìgbàkigbà tí ìkúùkù bá tó kúrò náà ni wọn ó tó gbéra.

Nọ́ḿbà 9

Nọ́ḿbà 9:11-23