Jóṣúà 1:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Jẹ́ alágbára, kí o sì mú àyà le; nítorí ìwọ ni yóò ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn wọ̀nyí; láti lè jogún ilẹ̀ tí mo ti búra fún àwọn baba ńlá a wọn láti fi fún wọn.

Jóṣúà 1

Jóṣúà 1:1-15