Jẹ́nẹ́sísì 36:26-30 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

26. Àwọn ọmọ Dísónì ni:Hémídánì, Ésíbánì, Ítíránì àti Kéránì.

27. Àwọn ọmọ Éṣérì:Bílíhánì, Ṣááfánì, àti Ákánì.

28. Àwọn ọmọ Díṣánì ni Húsì àti Áránì.

29. Àwọn wọ̀nyí ni olórí ìdílé Hórì:Lótanì, Ṣóbálì, Ṣíbéónì, Áná,

30. Dísónì Éṣérì, àti Díṣánì. Àwọn ni olórí ìdílé àwọn ará Órì gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn ní ilẹ̀ Ṣéírì.

Jẹ́nẹ́sísì 36