Àìsáyà 16:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà ni àwọn ará Móábù pohùnréréwọ́n jùmọ̀ pohùnréré lórí Móábù.Ṣunkún kí o sì banújẹ́fún àwọn ọkùnrin ìlú Hárésétì.

Àìsáyà 16

Àìsáyà 16:1-12