Neh 12:15-25 Yorùbá Bibeli (YCE)

15. Ti Harimu, Adna; ti Meraioti, Helkai;

16. Ti Iddo, Sekariah; ti Ginnetoni, Meṣullamu;

17. Ti Abijah, Sikri; ti Miniamini, ti Moadiah, Piltai:

18. Ti Bilga, Sammua; ti Ṣemaiah, Jehonatani;

19. Ati ti Joaribu, Mattenai; ti Jedaiah, Ussi;

20. Ti Sallai, Killai; ti Amoku, Eberi;

21. Ti Hilkiah, Haṣhabiah; ti Jedaiah, Netaneeli;

22. Ninu awọn ọmọ Lefi li ọjọ Eliaṣibu, Joiada, ati Johanani, ati Jaddua, awọn olori awọn baba: li a kọ sinu iwe pẹlu awọn alufa, titi di ijọba Dariusi ara Perṣia.

23. Awọn ọmọ Lefi, olori awọn baba li a kọ sinu iwe itan titi di ọjọ Johanani ọmọ Eliaṣibu.

24. Awọn olori awọn ọmọ Lefi si ni Haṣabiah, Ṣerebiah, ati Jeṣua ọmọ Kadmieli, pẹlu awọn arakunrin wọn kọju si ara wọn, lati yìn ati lati dupẹ, gẹgẹ bi aṣẹ Dafidi enia Ọlọrun, li ẹgbẹgbẹ ẹṣọ.

25. Mattaniah, ati Bakbukiah, Obadiah, Meṣullamu, Talmoni, Akkubu, jẹ adèna lati ma ṣọ ìloro ẹnu-ọ̀na.

Neh 12