Neh 10:20-29 Yorùbá Bibeli (YCE)

20. Magpiaṣi, Meṣullamu, Hasiri,

21. Meṣesabeeli, Sadoku, Jaddua,

22. Pelatiah, Hanani, Anaiah,

23. Hoṣea, Hananiah, Haṣubu,

24. Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,

25. Rehumu, Hasabna, Maaseiah,

26. Ati Ahijah, Hanani, Anani,

27. Malluku, Harimu, Baana.

28. Ati awọn enia iyokù, awọn alufa, awọn ọmọ Lefi, awọn adèna, awọn akọrin, awọn Netinimu, ati gbogbo awọn ti o ya ara wọn kuro lọdọ awọn enia ilẹ na si ofin Ọlọrun, aya wọn, awọn ọmọ wọn ọkunrin, ati awọn ọmọ wọn obinrin, gbogbo ẹniti o ni ìmọ ati oye;

29. Nwọn faramọ awọn arakunrin wọn, awọn ijoye wọn, nwọn si wọ inu èpe ati ibura, lati ma rìn ninu ofin Ọlọrun, ti a fi lelẹ nipa ọwọ Mose iranṣẹ Ọlọrun, lati kiyesi, ati lati ṣe gbogbo aṣẹ Jehofah, Oluwa wa, ati idajọ rẹ̀, ati ilana rẹ̀;

Neh 10