Mat 25:1-3 Yorùbá Bibeli (YCE)

1. NIGBANA li a o fi ijọba ọrun wé awọn wundia mẹwa, ti o mu fitila wọn, ti nwọn si jade lọ ipade ọkọ iyawo.

2. Marun ninu wọn ṣe ọlọgbọn, marun si ṣe alaigbọn.

3. Awọn ti o ṣe alaigbọ́n mu fitila wọn, nwọn kò si mu oróro lọwọ:

Mat 25