2. Kro 9:30-31 Yorùbá Bibeli (YCE)

30. Solomoni si jọba ni Jerusalemu lori gbogbo Israeli li ogoji ọdun.

31. Solomoni si sùn pẹlu awọn baba rẹ̀, a si sìn i ni ilu Dafidi baba rẹ̀: Rehoboamu, ọmọ rẹ̀ si jọba ni ipò rẹ̀.

2. Kro 9