1. Kro 11:25-39 Yorùbá Bibeli (YCE)

25. Kiyesi i, o li ọla jù awọn ọ̀gbọn lọ, ṣugbọn kò to awọn mẹta iṣaju. Dafidi si fi ṣe olori awọn igbimọ ile rẹ̀.

26. Awọn akọni ọkunrin ọmọ ogun rẹ̀ ni Asaheli arakunrin Joabu, Elhanani, ọmọ Dodo, ara Betlehemu.

27. Sammotu, ara Harori, Helesi, ara Peloni,

28. Ira, ọmọ Ikkeṣi, ara Tekoa, Abieseri ara Anatoti,

29. Sibbekai, ara Husa, Ilai, ara Ahohi,

30. Maharai, ara Netofa, Heledi ọmọ Baana, ara Netofa.

31. Itai ọmọ Ribai ti Gibea, ti awọn ọmọ Benjamini, Benaiah ara Piratoni,

32. Hurai ti odò Gaaṣi, Abieli ara Arbati,

33. Asmafeti ara Baharumi, Eliaba ara Ṣaalboni.

34. Awọn ọmọ Haṣemu ara Gisoni, Jonatani ọmọ Sage, ara Harari.

35. Ahihamu ọmọ Sakari, ara Harari, Elifali ọmọ Uri,

36. Heferi ara Mekerati, Ahijah ara Peloni,

37. Hesro ara Karmeli, Naari ọmọ Esbai,

38. Joeli arakunrin Natani, Mibhari ọmọ Haggeri,

39. Saleki ara Ammoni, Naharai ara Beroti, ẹniti nru ihamọra Joabu ọmọ Seruiah,

1. Kro 11