Gẹn 46:6 Yorùbá Bibeli (YCE)

Nwọn si mú ẹran wọn, ati ẹrù wọn, ti nwọn ní ni ilẹ Kenaani, nwọn si wá si Egipti, Jakobu, ati gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ pẹlu rẹ̀:

Gẹn 46

Gẹn 46:1-10