Gẹn 26:15 Yorùbá Bibeli (YCE)

Nitori gbogbo kanga ti awọn ọmọ-ọdọ baba rẹ̀ ti wà li ọjọ́ Abrahamu, baba rẹ̀, awọn ara Filistia dí wọn, nwọn si fi erupẹ dí wọn.

Gẹn 26

Gẹn 26:12-19