Samuẹli Kinni 22:1 BIBELI MIMỌ (BM)

Dafidi sá kúrò ní ìlú Gati, lọ sinu ihò òkúta kan lẹ́bàá Adulamu. Nígbà tí àwọn arakunrin rẹ̀ ati ìdílé baba rẹ̀ gbọ́, wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ̀.

Samuẹli Kinni 22

Samuẹli Kinni 22:1-8