Samuẹli Keji 19:10 BIBELI MIMỌ (BM)

A fi àmì òróró yan Absalomu ní ọba, ṣugbọn wọ́n ti pa á lójú ogun, nítorí náà, ó yẹ kí ẹnìkan gbìyànjú láti mú Dafidi ọba pada.”

Samuẹli Keji 19

Samuẹli Keji 19:1-14