Orin Dafidi 34:17 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí olódodo bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́, OLUWA a máa gbọ́,a sì máa gbà wọ́n kúrò ninu gbogbo ìyọnu wọn.

Orin Dafidi 34

Orin Dafidi 34:8-22